Font Size
Ìṣe àwọn Aposteli 10:36
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 10:36
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
36 Ẹyin mọ ọrọ̀ tí Ọlọ́run rán sí àwọn ọmọ Israẹli láti kéde ìròyìn ayọ̀ àlàáfíà nípasẹ̀ Jesu Kristi, ẹni ti ṣe Olúwa ohun gbogbo
Read full chapter
Romu 10:15
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Romu 10:15
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
15 (A)Wọ́n ó ha sì ti ṣe wàásù, bí kò ṣe pé a rán wọn? Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Ẹsẹ̀ àwọn tí ń wàásù ìhìnrere àlàáfíà ti dára tó, àwọn tí ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ohun rere!”
Read full chapter
Efesu 6:15
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Efesu 6:15
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
15 (A)Tí ẹ sì ti fi ìmúra ìhìnrere àlàáfíà wọ ẹsẹ̀ yín ní bàtà.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.