Font Size
Matiu 11:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 11:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 Àní kí ní ẹ jáde láti lọ wò? Wòlíì? Bẹ́ẹ̀ ni, mo wí fún yín, ó sì ju wòlíì lọ.”
Read full chapter
Matiu 14:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 14:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
5 (A)Herodu fẹ́ pa Johanu, ṣùgbọ́n ó bẹ̀rù àwọn ènìyàn nítorí gbogbo ènìyàn gbàgbọ́ pé wòlíì ni.
Read full chapter
Luku 1:76
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 1:76
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
76 (A)“Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì Ọ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa pè ọ́:
nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe;
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.